BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ofin
Ipa wo ni àìsí aṣojú INEC níbi ìpàdé àpérò ADC yóò ní lórí ẹgbẹ́ òṣèlú náà?
16 Ìgbé 2026
Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìjọba ṣe yọ ẹ̀sùn fifi owó ṣèrànwọ́ fún ìgbẹ́sùnmọ̀mí kúrò nínú ẹjọ́ ti Malami ń jẹ́
16 Ìgbé 2026
Kí ni alága àjọ INEC ṣe tí MURIC ṣe yarí pé lílọ ni yóò lọ àmọ́ táwọn ọ̀dọ́ ìlú rẹ̀ ṣèwọ́de àtìlẹ́yìn fún un?
15 Ìgbé 2026
"Bí Ishmail tí iná gbé ní Ilorin ṣe ń kàwé, ló ń ṣiṣẹ́ láti jẹ́ èèyàn láyé, owó díẹ̀ tó rí ló fi ra Kọ̀ǹpútà tó gbiná"
15 Ìgbé 2026
Èèyàn bíi 400 rí ẹ̀wọ̀n he lórí ìbáṣepọ̀ wọn pẹ̀lú agbésùnmọ̀mí ní Naijiria
12 Ìgbé 2026
''Mi ò sọ pé àṣìṣe wà nínú òfin owó orí tuntun ilẹ̀ Nàìjíríà, wọ́n ṣì mí gbọ́ ni'' -Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ìṣúná
12 Ìgbé 2026
Ìdílé oyè fún Gómìnà Adeleke ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ Apetumodu tó ń ṣẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà lóyè
10 Ìgbé 2026
4:00
Fídíò,
Soun Ogbomoso ti pín ìlú yẹ́lẹyẹ̀lẹ pẹ̀lú ìwà kíìgbọ́-kìígbà rẹ̀, èmi ò sì lè báa ṣiṣẹ́ mọ́ ni mo ṣe kọ̀wé fipò Máyégún sílẹ̀ -Sẹ́nétọ̀ Adeseun
, Duration 4,00
10 Ìgbé 2026
Ọkùnrin kan ṣekúpa èèyàn mẹ́ta nínú ìdílé kan náà, ariwo sọ
10 Ìgbé 2026
Ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilẹ̀, ilé ìtura, àtàwọn dúkìá míì tí wọ́n ní pásítọ̀ fi ọ̀nà èrú kó jọ
4 Ìgbé 2026
Kí ló dé tí ìjọba àpapọ̀ fi ₦9trn kún owó ìṣúná ọdún 2026?
3 Ìgbé 2026
ADC ní alága INEC ti gbàbọ̀dè, awọn fẹ́ kó kọ̀wé fipò sílẹ̀, APC fèsì pé kò sẹ́ni tó kó ba wọn, fúnra ara wọn, ni wọ́n ń ṣera wọn
3 Ìgbé 2026
Àwọn ìgbésẹ̀ wo ló yẹ fún iléeṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ láti gbé kí wọ́n tó ta síìmù ìpè ti ẹnìkan ti lò rí fún ẹlòmíì?
1 Ìgbé 2026
ICPC tú El-Rufai sílẹ̀ lẹ́yìn tó pàdánù ìyá rẹ̀
28 Ẹrẹ̀nà 2026
NBA,Ẹgbẹ́ Amòfin Naijiria bínú sí Sowore tó pàtẹ ìpàdé akọ̀ròyìn nínú kóòtù
25 Ẹrẹ̀nà 2026
Kò tí ì sí obìnrin kankan tó jáde síta pé wọ́n fipá bá òun lòpọ̀ lásìkò ọ̀dun Ozoro - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá
23 Ẹrẹ̀nà 2026
Ọ̀dọ́kùnrin ẹni ọdún 21 fipá bá obìnrin lopọ̀, fún un lọ́rùn pa l'Ondo
23 Ẹrẹ̀nà 2026
Ẹ̀yin aráàlú, ẹ láṣẹ láti ya fídíò àwọn ọlọ́pàá lẹ́nu iṣẹ́, wọ́n sì gbọdọ̀ lẹ orúkọ wọn sáyà - Adájọ́
19 Ẹrẹ̀nà 2026
Ìdí rèé tí Bàbá Mohbad ṣe tako ibùdó àyẹ̀wò ẹ̀jẹ̀ tí wọn ti fẹ́ ṣe DNA fún Liam ọmọ Mohbad nílùú òyìnbó
19 Ẹrẹ̀nà 2026
Adájọ́ pàṣe kí agbẹjọ́rò Sowore kúnlẹ̀ torí àrífín, agbẹjọ́rò ní ó di ayé àtúnwá
18 Ẹrẹ̀nà 2026
Àwọn ẹlẹ́rìí EFCC sọ fún ilé ẹjọ́ bí ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù ṣe wọ akoto owó tó nííṣe pẹ̀lú Malami
18 Ẹrẹ̀nà 2026
Fídíò ‘Sharwama’, ọkùnrin tó ní òun ti pa èèyàn 32 gba orí ayélujára, Ọlọ́pàá Oyo sọ̀rọ̀
18 Ẹrẹ̀nà 2026
Ọwọ́ àjọ NDLEA tẹ bàbá ẹni ọdún 74 pẹ̀lú oogun olóró l'Abuja
15 Ẹrẹ̀nà 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology