BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ofin
Gómìnà Adeleke gbé ìgbìmọ̀ dìde láti ṣe ìwádìí àwọn ìpànìyàn tó wáyé nílùú Ikire
30 Ògún 2026
Àwọn mọ̀lẹ́bí àwọn tó kú níbí ìkọlù Ikire n bèèrè fín ìdájọ́ òdodo
29 Ògún 2026
Èèyà mẹ́ta farapa níbi tí ọlọ́pàá ti yìnbọn pa awakọ̀ lásìkò àyẹ̀wò
29 Ògún 2026
4:55
Fídíò,
Ẹlẹ́mí èṣù làwọn ayálégbé míràn, àfi kí ìjọ̀ba yọwọ́ lọ́rọ́ onílé àti ayálégbé ní Nàìjíríà – Isaac Fayose
, Duration 4,55
29 Ògún 2026
4:03
Fídíò,
Àwọn 'ọlọ́pàá' tó fẹ́ wá fi tipá gbé mi gbá ìdí ìbọn gbá ìyàwó mi, wọ́n sì bá oyún inú rẹ̀ jẹ́ – Tani Olohun
, Duration 4,03
28 Ògún 2026
Ìrírí mi nígbà àkọ́kọ́ tí wọ́n gbé mi lọ sí Ilorin jẹ́ kí n mọ̀ pé àwọn tó wá fi tipá gbé mi lè pa mí – Tani Olohun
28 Ògún 2026
Bílíọ̀nù mẹ́jọ Naira làwọn ajínigbé ti gbà lọ́wọ́ aráàlú láàrín ọdún 2025 sí 2026 - Ìwádìí
27 Ògún 2026
Òkú sùn, dúkìá ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù bàjẹ́ lásìkò táwọn awakọ̀èrò gbìyànjú láti gba gáréèjì ní Ikire
24 Ògún 2026
Afẹnifere figbeta pé àfikún ti ba ìjínigbé, ìpànìyàn àti ìkọlù tó ń kojú àwọn àgbẹ̀ ilẹ̀ Yorùbá
22 Ògún 2026
Wo gbèdéke owó tí òfin là kalẹ̀ fún olùdíje sípò ààrẹ, gómìnà àtàwọn olùdíje míì láti ná fún ìpolongo ìbò 2027
20 Ògún 2026
A máa tá tán ni pẹ̀lú Tani Olorun, nínú kó lọ sẹ́wọ̀n tí ọwọ́ òfin bá tẹ̀ ẹ́, tàbí ká fìdí rẹ̀mi - Agbejọ́rò Imam
19 Ògún 2026
Sẹ́nétọ̀ Osun wọ gàù lẹ́yìn tó ní kí àwọn alátìlẹyìn òun máa pa àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú Accord lọ́jọ́ ìbò
12 Ògún 2026
Àgbékalẹ̀ ètò agbófinró tí kò ní ṣe ojúṣàájú fún ẹnikẹ̀ni ni ìjọba ń fẹ́ – Fagbemi
8 Ògún 2026
Báwo ni àjọ ICPC tún ṣe ṣàwárí ilé-iṣẹ́ ayédèrú méjì míràn tí Adeyemi Adeniyi dá sílẹ̀?
7 Ògún 2026
Adeleke wọ́ báǹkì First Bank àti EFCC lọ sílé-ẹjọ́ lórí àkáǹtì ìjọba Osun tí wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé
7 Ògún 2026
Àlàyé rèé lórí ìdí tí báálé ilé ṣe ju ọmọ rẹ̀ méjì sílẹ̀ láti orí ilé alájà mẹ́ta, tó tún fẹ́ ju ìyá wọn náà tẹ̀le
5 Ògún 2026
Oriyomi Hamzat kò kópa nínú ìdìbò abẹ́nú Accord, ẹ yọ ọ́ kúrò bíi olùdíje gómìnà - Busari Gudugúdù wọ́ ẹgbẹ́ òṣèlu Accord àti INEC lọ sílé-ẹjọ́
4 Ògún 2026
PFIPC: Kìí ṣe Adeyemi nìkan ló ṣe ohun tí wọ́n fẹ̀sùn rẹ̀ kàn án, ọ̀pọ̀ èèyàn nínú ìjọba ló lọ́wọ́ si - Agbẹjọ́rò
3 Ògún 2026
Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí fídíò tó ṣàfihàn báwọn ọlọ́pàá kan ti ṣe ìkọlù sí ọ̀dọ́kùnrin tó ń ta góòlù l'Eko
2 Ògún 2026
Ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá gbé ọ̀gá ọlọ́pàá tuntun lọ sí ìpínlẹ̀ Osun ṣáájú ìdìbò gómìnà tó n bọ̀
1 Ògún 2026
Ìbẹ̀rù-bojo gbalẹ̀ l'Osun ṣáájú ìbò gómìnà tó ń bọ̀, ọlọ́pàá mú akọ̀wé ijọba, Adeleke ní aráàlú kò ní gbà
30 Agẹmo 2026
Kílódé tí ọtí pẹlẹbè ṣì pọ̀ ní ìgboro bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìjọba ti gbẹ́sẹ̀ le?
29 Agẹmo 2026
Ọmọ Nàìjíríà míràn tún kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá ní South Africa; Ìjọba Nàìjíríà fárígá, pè fún ìwádìí kíkún
27 Agẹmo 2026
5:16
Fídíò,
Àdó olóró àwọn ajínigbé pa Shuaibu aṣọ́gbóọba lásìkò tó ń lé àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé ní Oriire, àwọn ẹbí rẹ̀ pariwo síta
, Duration 5,16
27 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology