BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Àwọn ajínigbé ṣekúpa sọ́jà, Amotekun, ọlọ́dẹ àti olùkọ́ méjì nínú igbó, Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ Esinele sọ ìdí tí wọ́n fi pa àwọn olùkọ́
Arabinrin Alamu ni ''awọn ajinigbe naa dẹru ba wa, wọn tun sọ wa pe ijọba ti gbagbe wa sinu igbo.
Wo orílẹ́èdè 62 táwọn èèyàn ibẹ̀ kò nílò fisà láti wọ orílẹ́èdè Germany
Gẹgẹ bii atẹjade ti ẹka ijọba orilẹede Germany to n ri si ọrọ ilẹ okeere fi sori itakun agbọrọkaye wọn, awọn eeyan lati orilẹede mejilelọgọta yii lanfaani lati ṣabẹwo si Germany fun aadọrun un ọjọ fun irinajo igbafẹ, ipade okoowo ati igbadun ẹbi.
Fídíò, 'Kò síná, kò sómi, àfi bí pé ìhòhò la wa ni, ọmọ ọdún méje kò fojú rínà ọba rí nílùú yìí', Duration 2,21
Wọn ni o ti to ọdun mẹfa si meje ti wọn ti ri ina mọnamọna kẹyin ni ilu naa,
Ilé aṣòfin àgbà ní kí ìjọba yé dáríji àwọn agbéṣùmọ̀mí Boko Haram tó bá juwọ́ sílẹ̀ mọ́
Ile aṣofin agba fẹnuko lori igbesẹ yii nibi ijiroro to waye nile aṣofin lọjọ Iṣẹgun lori aba ti aṣofin Abdulaziz Yar'Adua fi siwaju ile lori awọn ikọlu to n waye lemọlemọ kaakiri Naijiria to fi mọ ijinigbe ati ipaniyan.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 0,59
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́
Ìjọba àpapọ̀ wọ́gilé àfikún owó ìdánwò WAEC àti NECO tó ṣe láti ₦27,500 sí ₦50,000
Ninu atẹjade kan ti ileeṣẹ ijọba to n ri si eto ekọ ni Naijiria fi lede, ijọba ni oun gbe igbesẹ yii lọna ati kọkọ jiroro pẹlu awọn ti ọrọ kan lori igbesẹ ọhun.
Wo ọ̀nà márùn-ún tí àwọn ọ̀dọ́ lè máa gbà rí owo gọbọi
Bi eeyan tiẹ ba ọla nile paapaa, to ri ogun gidi to le sọ di owo jẹ lọdọ awọn obi rẹ, dandan tun ni ko ṣiṣẹ kun un ki ọrọ naa ma baa parun.
Alága àdúgbò dá baálé ilé dọ́bálẹ̀, fi pankẹ́rẹ́ dá sẹ̀ríà ìyà fún un torí pé ó sọ̀rọ̀ lórí àṣepatì àkànṣeiṣẹ́ àjọ NDDC, ọlọ́pàá ní iléẹjọ́ yá
Atẹjade kan ti ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Delta fi sita lo fidi ẹ mulẹ, pe awọn eeyan naa huwa to lodi sofin, igbejọ si ti bẹrẹ lori ọrọ wọn.
Àlàyé lóríi bí àjọ NDLEA ṣe mú afurasí ọmọ South Africa kan l'Abuja lórí ẹ̀sùn pé ó gbé oògùn olóró Heroin
NDLEA ni ọmọ ọdun mẹta ti arabinrin naa gbe lọwọ lo fẹ fi boju ki aṣiri rẹ ma baa tu nibi ti wọn ti n ṣayẹwo fun un ni papakọ ofurufu ilu Abuja.
Sunday Igboho sọ ìdí tí ìjọba ṣe kọ̀ láti sanwó ìtúsílẹ̀ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso
Ninu atẹjade kan ti Igboho fi lede lati ọwọ agbẹnusọ rẹ lo ti sọrọ naa.
Iléẹṣẹ́ ológun Nàìjíríà ṣàlàyé iṣẹ́ oṣù kan tí wọ́n fi gba akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn olùkọ́ Oríire lọ́wọ́ ajínigbé
Ọgagun Danjuma Jonah Danjuma, ti ẹka ikede nileeṣẹ ologun ẹkun keji (2 Division) lo fi atẹjade to ṣalaye ọna tawọn to wa nigbekun naa gba ri itusilẹ lọjọ kẹwaa, oṣu Keje ọdun 2026.
Èyí ni àpéjọpọ̀ ẹ̀sìn márùn-ún táwọn èèyàn ti máa ń pọ̀jù lágbàáyé
Lọwọlọwọ yii, apejọpọ marun-un lo jẹ koko ti wọn si gbajumọ ju lagbaaye, eyi to jẹ ti ẹsin.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Mo lè má sí láyé láti kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2027 – Obi
Gomina tẹlẹri nipinlẹ Anambra sọ pe ọpọ awọn ẹtọ oun ni ijọba ilẹ Naijiria fi n dunkooko mọ oun, ati pe gbogbo awọn to duro gẹgẹ bi alatako ijọba ni wọn n dojukọ idunkooko loriṣiriṣi.
Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ondo gbẹ̀mí afurasí ajínigbé méjì lójú ọ́nà Owo lẹ́yìn tí wọ́n ṣíná ìbọn fúnra wọn
Ọlọpaa ni awọn ri ibọn ilewọ agbelẹrọ meji, ọta ibọn, awọn iboju meji, ẹrọ ilewọ ati kaadi ATM lakata wọn lẹyin ikọlu naa.
Àwọn afurasí tò ṣekúpa òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì OGTV fojú ba ilé ẹjọ́, bí ìgbẹ́jọ́ ṣe lọ rèé
Kitan Oyesiku ati ẹṣọ alaabo rẹ, Pelumi Adetayo ni awọn amookunṣeka naa pa nipakupa laipẹ yii niluu Kobape to wa loju ọna marosẹ Abeokuta si Sagamu.
Aṣojú ìjọba Nàìjíríà nílẹ̀ Olómìnira Benin gba àlejò ọkùnrin tó gun ọ̀kadà láti London wá sí Nàìjíríà
Ọjọ kejila, oṣu Kẹfa ọdun 2026 yii ni Olatunji Emmanuel Okedeyi gbera kuro niluu London.
Ìjìyà tó bá tọ́ sí agbésùnmọ̀mí la máa fún ṣọ́jà tó bá ń dúró de àṣẹ kó tó pa wọ́n- Mínísítà ètò ààbò
Ipinlẹ Sokoto ni Ọgagun Musa ti sọrọ yii, lasiko ti wọn n pin awọn ọkọ akọtami fawọn ẹka alaabo .
Amẹ́ríkà àti Iran tún ju àdó olóró síra, èèyàn mẹ́rìnlá jáde láye
Amẹrika ni awọn ṣe ikọlu si ibudo awọn oloogun Iran to jẹ aadọrun-un. Iran sọ pe eeyan mẹrinla ni Amẹrika ti pa lẹnu ikọlu ọjọ meji naa.
Àjọ EFCC wọ́ olórí ẹgbẹ́ Miyetti Allah lọ sílé-ẹjọ́ lórí ẹ̀sun jìbìtì $2.3m
Ẹsun mejila ọtọọtọ to nii ṣe pẹlu iwa ajẹbanu ni ajọ naa fi kan Miyetti Allah niwaju ile-ẹjọ, eyi ti wọn sọ pe wọn tẹwọ gba obitibiti owo ilẹ okeere ọhun, ti wọn lo lodi si ofin.
Ẹṣin mọ́kàndínláàádọ́ta ni mo ti pàdánù ní iléeṣẹ́ mi - Ibrahim Chatta
Chatta ninu fidio kan to fi sori ikanni Instagram rẹ, sọ pe oun sọrọ sita lori iṣẹlẹ naa lẹyin ti awọn eeyan n fi oun ṣe yẹyẹ lori ọrọ naa lori ayelujara.
Agbèsùnmọ̀mí pa ṣọ́já, dàná sun àgọ́ ọlọ́pàá, iléèwòsàn àti yàrá ìkàwé
Adele Alukoro fun ẹka ologun apapọ lapa Ariwa-Ila-Oorun Naijiria, Ọgagun Muhammed Goni, fidi ikọlu naa mulẹ ninu atẹjade to fi sita l'Ọjọbọ, ọjọ kẹsan-an oṣu Keje ọdun 2026 yii.
Ẹ má ṣe kọ̀ láti gba ọgọ́rùn-ún kan náírà, ìjìyà wà fún ẹni tó bá kọ̀ ọ́ – Báǹkì àpapọ̀ Naijiria kìlọ̀ fùn aráàlú
CBN sọ pe ki gbogbo awọn to n kọ lati maa gba owo ọgọrun kan naira naa dẹkun iwa naa bayii, nitori pe owo ọhun ṣi n jẹ itẹwọgba labẹ aṣẹ, akoso ati ofin ilẹ Naijiria.
Báwo ni owó PFIPC ṣe wọ́ àbá ìsúná tó bá jẹ́ ìjọba kò mọ nípa àjọ náà lóòótọ́, èmi kọ́ ni mo ṣé e, mo wà ní àhámọ́ ọlọ́pàá lásìkò náà - Adeyemi sọ nínú fídíò tuntun
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara ṣafihan bi Adeyemi ṣe n ba gbajumọ ori ayelujara, Martins Otse ti ọpọ eeyan mọ si VeryDarkMan sọrọ.
Ifá kìlọ̀ fáwọn olóṣèlú tó fẹ́ dupò gómìnà l'Osun, àlàyè rèé
Ẹgbẹ naa ti orukọ wọn n jẹ Traditional Religion Worshippers Association of Osun State (TRAWSO), ṣekilọ yii lasiko ti wọn n ba awọn akọroyin sọrọ niluu Oṣogbo lọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Davido ṣàlàyé ìdí tó fi wọ aṣọ tórúkọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso wà lára rẹ̀ níbí ìdíje World Cup
Davido sọ fun BBC News Africa wi pe ko ṣee ṣe ki oun kọ eti ikun si eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria papaa julọ ijinigbe awọn akẹkọọ mọkandinlogoji atawọn olukọ meje to ṣẹlẹ ni ijọba ibilẹ Oriire nipinlẹ Oyo.
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Sam Larry níbi tí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ Adewale ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀
Ninu ibanujẹ ọkan ni ẹbi Adewale, ẹṣọ Sam Larry to ku ninu ijamba ọkọ to ṣẹlẹ lopopona marosẹ Eko si Calabar wa bayii.
IMF fẹ̀sùn kan ìjọba àpapọ̀ pé ó ná ₦N8.83trn tí kò ní àkọsílẹ̀, ìjọba ṣẹ́, Peter Obi àti Atiku ní kí Tinubu fi ipò sílẹ̀
Aṣoju ajọ IMF ni Naijiria, Christian Ebeke, sọ niluu Eko pe nnkan bii ida meji owo ti ijọba Naijiria na ni ko si akọsilẹ rẹ rara, bo tilẹ jẹ pe o yẹ ki akọsilẹ rẹ wa.
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ
Ọlọpaa sọ pe ikọlu ti eegun naa atawọn ọmọ ẹyin rẹ si si ọkunrin naa lo pa a lọjọ Aiku, ọjọ karun-un oṣu Keje ọdun 2026.
Ọmọ ọdún méjìlélógún ṣàlàyé bó ṣe jí ara rẹ̀ gbé, tó sì ń bèèrè N25m owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ẹbí rẹ̀
James ninu fidio kan ti Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Delta, Bright Edafe fi sita lọjọ Aiku, ṣalaye pe oun mọ-ọn-mọ wọgbo lọ, oun si pe iya oun lori aago pe wọn ti ji oun gbe.
Ìjọba àpapọ̀ kéde ìpínlẹ̀ 26 tí òjò àrọ̀rọ̀dá yóò ti wáyé fún ọ̀sẹ̀ méjìlá èyí tí yóò fa ẹ̀kún omi
Adari ajọ NiHSA Umar Mohammed, ni awọn ti kilọ fun awọn ọmọ Naijiria ṣaaju iṣẹlẹ ọhun amọ gbogbo ikilọ awọn ni araalu kọ eti ọgbọin si.
Àṣírí ti tú nípa àwọn tó wà nídìí ìjínigbé akẹ́kọ̀ọ́ àti Olùkọ́ Esinele, ìbẹ̀rù ti ń báwọn ajínígbé náà, a ti mọ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ wọn - Ẹ̀ṣọ́ aláàbò
Gẹgẹ bi awọn ẹka ẹṣọ aabo ṣe n fidi ẹ mulẹ, wọn ni ẹkọ ti n fi oju mimu han lẹyin ti wọn ti mọ awọn to wa nidii ijinigbe naa, atawọn alajọṣiṣẹ pọ wọn.
Mo ta ‘Pure Water’ láti rán ara mi nílé ẹ̀kọ́ àmọ́ ń kò parí rẹ̀, èmi tí wọ́n ń pè ní Olódo tẹ́lẹ̀, ló ń bọ́ bàbá àti ẹbí mi báyìí - Portable
Portable sọrọ yii ninu ifọrọwanilẹnuwo kan ti o ṣe pẹlu awọn akọroyin ori itakun ayelujara.
Awuyewuye bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn tí àdó olóró pa ọmọ Nàíjíríà tó n kẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ ìṣègùn òyìnbó ní Ukraine
Nnani la gbọ pe o ki aye pe o digboṣe lẹyin to fara kaaṣa ado oloro ti awọn ọmọ ogun orileede Russia ju si ilẹ Ukraine lasiko ikọlu.
Kí ni àyájọ́ 7-7 túmọ̀ sí àti itú tàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn le pa láti sàmì àyájọ́ náà
Atẹjade ti ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ati Osun fisita lori ayajọ ẹgbẹ okunkun 7-7, ti wa n sin awọn araalu ni gbẹrẹ ipakọ pe ki wọn fura nipa ọsẹ tawọn ẹlẹgbẹ okunkun naa le se.okunkun naa le se.
Ojú mi rí màbo láti kékeré títí mo fi délé ọkọ, mo fẹ́ pa ègún, tó ja ìyá mi àti èmi rẹ́ lórí ọmọ - Iyabo Ojo
Iyabo Ojo ṣalaye pe ipinya oun ati ọkọ toun bimọ fun ko kan awọn tawọn bi.













































































