BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Èèyàn bíi 400 rí ẹ̀wọ̀n he lórí ìbáṣepọ̀ wọn pẹ̀lú agbésùnmọ̀mí ní Naijiria
Lara awọn idajọ ti awọn afurasi naa gba ni idajọ ẹwọn ọdun marun un si ẹwọn gbere fun ibaṣepọ wọn pẹlu ẹgbẹ agbesunmọmi Boko Haram ati ẹgbẹ Islamic State West Africa Province (Iswap) to yapa kuro ni Boko Haram.
Àdó olóró ológun òfurufú tí wọ́n ló pa ọ̀pọ̀ aráàlú nínú ọjà ní Yobe, ohun tí a mọ̀ rèé
Koda, yatọ si awọn to farapa, a gbọ pe eeyan to le ni ogun (20) lo tun di oloogbe ninu iṣẹlẹ ojiji naa.
''Mi ò sọ pé àṣìṣe wà nínú òfin owó orí tuntun ilẹ̀ Nàìjíríà, wọ́n ṣì mí gbọ́ ni'' -Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ìṣúná
Ninu atẹjade ti 'Presidential Fiscal Policy and Tax Reforms' fi sita lọjọ Aiku ni minisita naa ti sọ pe iroyin to le ṣi araalu lọna ni wọn n gbe kiri.
Ìjíròrò láàárín Amẹ́ríkà àti Iran láti fòpin sí ogun forí sánpọ́n
Ìlú Islamabad, olú ìlú orílẹ̀ èdè Pakistan ni wọ́n fẹnukò pé kí ìjíròrò náà ti wáyé lẹ́yìn ìgbésẹ̀ ààrẹ Pakistan àti ààrẹ China dá sí ìkọlù tó ń wáyé náà.
Agbéṣùmọ̀mí kọ lẹ́tà sáwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Katsina, bèèrè màlúù 700, àgùtàn 1,000
Ibeere yii lo wa ninu lẹta kan ti awọn agbesunmọmi naa fi ṣọwọ si awọn ilu ti ọrọ naa kan lọjọ kẹfa, oṣu Kẹrin, ọdun 2026 ti a wa yii.
Àwọn afurasí jàndùkú agbébọn ṣekúpa ìyá àti ọmọ l'Ondo
Iṣẹlẹ yii lo tun ti fa ibẹru bojo bayii ni agbegbe naa, bi awọn eniyan se n sa asala fun ẹmi wọn, ti wọn si n kọminu lori ipo ti ọrọ eto aabo wa ni Ipinlẹ Ondo.
Ààrẹ Omar Guelleh tún wọlé sáà kẹfà ní Djibouti, lẹ́yìn ọdún 27 tó ti wà nípò
Ọpọ awọn to yẹ ki wọn jọ dupo aarẹ naa ni ko ba wọn kopa, awijare wọn si ni pe ko si akoyawo ninu idibo orilẹede naa mọ.
Ìjọba yóò máa gba ìwé ìrìnnà lọ́wọ́ àwọn tó bá ní àwọn kì í ṣe ọmọ Naijiria mọ́
Atẹjade naa ṣalaye pe awọn eeyan ti Aarẹ ba ti gba pe awọn ki i ṣe ọmọ Naijiria mọ ni ọrọ yii kan.
Àwọn agbẹ́bọn tún pa ọ̀dọ́ l'Ondo, aráàlú fi ẹ̀hónú hàn
Lati le fopin si ikọlu ati ijinigbe tó n waye lemọlemọ naa, ati lati kesi ijọba fun ojutuu lo jẹ kawọn olugbe agbegbe yii gbegi di opopona to lọ si ofiisi Gomina, niluu Akure, lati fi ehonu han.
Ìjọba Nàìjíríà kéde orúkọ àwọn afurasí tó ń ran ìgbésùnmọ̀mí lọ́wọ́
Igbimọ 'Nigeria Sanctions Committee' (NSC) to gbe awọn orukọ naa jade ko sọ ọmọ orilẹede ti wọn jẹ, bẹẹ ni ko ṣalaye bi ipa ti wọn ti ko ninu igbesunmọmi ṣe pọ to.
Póòpù ń ṣàbẹ̀wò sílẹ̀ Africa pẹ̀lú ìwáásù àlááfíà àti ìṣọ̀kan
Àbẹ̀wò Pope Leo XIV sílẹ̀ Africa yìí ló máa jẹ́ ìrìnàjò rẹ̀ tó gùn jùlọ láti ìgbà tó ti di póòpù ìjọ Àgùdà.
Fídíò, Kí ló sọ àwọn ológbò di gbajúmọ̀ orí ayélujára ní Instabul?, Duration 1,25
Níṣe ni àwọn ológbò ti di gbajúmọ̀ lórí ayélujára báyìí bí ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn tó ń rìnrìnàjò afẹ́ lọ sí Instabul ṣe ń tò láti bá àwọn ológbò yàwòrán.
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ìdílé oyè fún Gómìnà Adeleke ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ Apetumodu tó ń ṣẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà lóyè
Ile ẹjọ kan lorilẹede Amẹrika lo dajọ ẹwọn fun Ọba Apetumodu ti ilu Ipetumodu ti wọn ni o jẹbi ẹsun lilu jibiti pẹlu eto ẹyawo COVID-19 ti wọn gbe kalẹ lati ṣe iranwọ fun awọn okoowo kekeke to fara kaasa lasiko ajakalẹ arun naa.
Ìjọba àpapọ̀ ké gbàjarè lẹ́yìn tí àrùn tó ń gbẹ̀mí màlúù kọlu ìpínlẹ̀ 17
Ijọba ni arun naa n ṣakoba fun ọrọ aje ohun ọsin ati pe ti ijọba ko ba tete kapa rẹ, o le pa odidi agbo maluu kan run.
Ta ni ọ̀gágun Braimah táwọn agbésùnmọ̀mí ṣekúpa pẹ̀láwọn ọmọogun míràn ní Borno, Tinubu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn tó ṣubú lójú ìjà?
Ohun ti a gbọ ni pe lojiji lawọn agbesunmọmi naa ya wọ ibudo awọn ọmogun naa ti wọn si bẹrẹ si ni yinbọn.
Wo bí o ṣe lè wo, tàbí ṣe àtẹ̀jáde ìwé atọ́nà pélébé fún ìdánwò Jamb UTME
Ajọ Jamb ni idanwonaa yoo ṣi waye laarin ọjọ kẹrindinlogun si ikarundinlọgbọn oṣu kẹrin ọdun 2025 ti wọn kede tẹlẹ.
Ọkùnrin kan ṣekúpa èèyàn mẹ́ta nínú ìdílé kan náà, ariwo sọ
Àwọn kan ń sọ pé ọkùnrin tó ṣá àwọn èèyàn náà ní àìsàn ọpọlọ ń dà láàmú ṣùgbọ́n BBC New Yoruba kò le fìdí èyí múlẹ̀.
Iléeṣẹ́ ìfọpo Dangote dá owó epo bẹntiró padà sí ₦1,200
Ileeṣẹ ọhun sọ ninu atẹjade kan pe adinku owo epo yii lo n waye latari bii owo epo naa ṣe n lọ soke ati sodo lagbaye.
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ aláàbò ilẹ̀ Ibadan tuntun, Ibadan Community Guard
Aafin Olubadan to wa ni Oke Aremo niluu Ibadan ni wọn ti ṣe eto naa.
Akẹ́kọ̀ọ́ Covenant University jáde láyé níbi tó ti ń gbá bọ́ọ̀lù, Ilé ẹ̀kọ́ ṣàlàyé ohun tó fa ikú rẹ̀
Ìròyìn tó gba orí ayélujára ni pé lásìkò tí akẹ́kọ̀ọ́ náà ń kópa nínú bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ló déédé ṣubú lulẹ̀, tí kò sì tètè rí ìtọ́jú tó fi gba ibẹ̀ jáde láyé.
Amẹ́ríkà gbé ìkìlọ̀ tuntun jáde lórí ọ̀rọ̀ àbò ní Nàìjíríà, Ó ní ìlú Abuja àtàwọn ìpínlẹ̀ 23 kan ti di ibi àìgbọdọ̀ wọ̀ fáwọn èèyàn rẹ̀, ìdí rèé
Ni irọlẹ Ọjọru ọjọ kẹjọ oṣu Kẹrin ọdun yii ni ileeṣẹ ijọba Amẹrika to n ri si ọrọ ilẹ okeere fi ikilọ naa sita.
Ẹ múra o! Òjò ńlá tó le fa àgbárá òjò ń bọ̀ ní ìpínlẹ̀ mẹ́wàá - NiMet
Ninu atẹjade ti ajọ naa fi sita lọjọru ni wọn ti tun sọ pe iji yoo waye lawọn ipinlẹ kan nigba ti oorun yoo si jade lawọn ibomiran.
Àlàyé lórí ohun tó fa rògbòdìyàn inú ẹgbẹ́ ADC, èyí tó jẹ́ kí INEC yẹ àga máwọn adarí ẹgbẹ́ náà nídìí
Awuyewuye lori igbimọ adari ẹgbẹ oṣelu ADC bẹrẹ loṣu Keje ọdun 2025 nigba tawọn adari ẹgbẹ naa kọwe fipo silẹ ti David Mark si di alaga fidihẹ.
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ṣé lóòótọ́ làwọn ọmọ ogun máa ń ra aṣọ ogun àti ohun ààbò fúnra wọn?- iléeṣẹ́ ológun sọ̀rọ̀
Àtẹ̀jáde kan tí adelé adarí ẹ̀ka tó ń rí sí ọ̀rọ̀ aráàlú ní iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà, Appolonia Anele fi léde lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun sọ pé irọ́ tó jìnà sí òótọ́ ni ẹ̀sùn náà àti pé ó le ṣi ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́kàn.
Wáyà iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì já, iná ṣẹ́yọ, ṣekúpa èèyàn kan ní Ilọrin, ọ̀pọ̀ farapa, dúkìá olówó iyebíye jó mọ́lé
Àwọn èèyàn agbègbè náà ní ibi tí wọ́n ti ń gbìyànjú láti yọ ohun èlò kúrò lára iná ló ti gbé e.
Mi ò bá Makinde àti Olubadan jà, ìdí rèé táwọn èèyàn kò fi rí mi pọ̀ mọ́ Gómìnà àti Ọba Ladoja - Alaafin
Alaafin ni oun ni ibaṣepọ to dan mọran pẹlu Ọba Rashidi Ladoja ati Gomina ipinlẹ Oyo.
Wo àwọn ojú pópó tí yóò wà ní títì pa nílùú Eko lásìkò àbẹ̀wò Tinubu bẹ̀rẹ̀ láti òní
Kọmiṣọna fun igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, Oluwaseun Osiyemi, sọ ninu atẹjade kan to fi sita pe igbesẹ yii waye lati le jẹ ki eto ifilọlẹ awọn akanṣẹ iṣẹ ti Gomina Babajide Sanwo-Olu ti aarẹ fẹ ṣe lọ ni irọwọ rọsẹ.
Àwọn afurasí darandaran ṣá àgbẹ̀ sínú oko rẹ̀ l'Ogbomoso lẹ́yìn tó ní wọn kò gbọdọ̀ da ẹran níbẹ̀
Awọn afurasi darandaran naa ni wọn fẹ fi awọn maalu wọn jẹ oko oloogbe Kehinde lọjọ Isinmi, ọjọ karun un, oṣu Kẹrin ọdun 2026 yii, amọ o kọ jale ki wọn to gbẹmi rẹ.
Ṣé lóòótọ́ ni ìjà wà láàrin Tinubu àti Sanwo-Olu? Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko sàlàyé
Ijọba ipinlẹ Eko ni ''baba ni Aarẹ Bola Tinubu jẹ fun Sanwo-Olu, ati pe ahesọ ọrọ lasan ni gbogbo nnkan tawọn eeyan n gbe kiri.''
Kí ni yóò ṣẹlẹ̀ tí gbèdéke tí Trump fún Iran lórí 'Strait of Hormuz' bá kọjá?
Ó ní láti dènà irúfẹ́ ìkọlù yìí, Iran gbọdọ̀ gbà àwọn nǹkan tí òun ń fẹ́, tó fi mọ́ fífi ààyè gba gbígbé epo láì sí ìdàmú gba Strait of Hormuz.
Wo orílẹ̀èdè márùn-ún tí inú àwọn èèyàn rẹ̀ dùn jùlọ lágbàáyé lọ́dún 2026
Ìjábọ̀ náà, tí àjọ Oxford Health Research Institute pẹ̀lú àjọṣepọ̀ United Nations Sustainable Development Goals máa ń gbé jáde ní ọdọọdún, máa ń ṣe àgbéyẹ̀wò ètò ọrọ̀ ajé, àtìlẹyìn àwùjọ, bí àwọn èèyàn ṣe ní àǹfàní láti lè jáde bó bá ṣe wù wọ́n sí, àti bí ẹ̀mí àwọn èèyàn ṣe le gùn sí ní orílẹ̀ èdè ogóje (140) káàkiri àgbáyé yẹ̀wò.
A ti dóòlà èèyàn 31 tí wọ́n jí gbé nílé ìjọsìn lọ́jọ́ ọdún Àjínde – Ilésṣẹ́ ọmọ ogun
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọmọ ogun sọ pe awọn ko fi akoko ṣofo ki awọn to ya bo ile ijọsin ti ikọlu naa ti waye, awọn to wa nibẹ sọ fun awọn akọroyin pe fun ọpọ wakati lawọn agbesunmọmi naa fi ṣọṣẹ lai si idwọ kankan.











































































