BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Awọn ọdọ
Wọ́n na àwọn ọmọdé tó wà nínú wa, wọ́n fi aṣọ dí wọn lẹ́nu, wọ́n fi ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ sí àwọn ọkùnrin lẹ́sẹ̀ - Arábìnrin Alamu
14 Agẹmo 2026
Wo ọ̀nà márùn-ún tí àwọn ọ̀dọ́ lè máa gbà rí owo gọbọi
13 Agẹmo 2026
Nkò wẹ̀, nkò jẹun fún ọjọ́ mẹ́rin láhàámọ́ ọlọ́pàá - Peller, gbajúmọ̀ orí ayélujára
10 Agẹmo 2026
Mo ta ‘Pure Water’ láti rán ara mi nílé ẹ̀kọ́ àmọ́ ń kò parí rẹ̀, èmi tí wọ́n ń pè ní Olódo tẹ́lẹ̀, ló ń bọ́ bàbá àti ẹbí mi báyìí - Portable
7 Agẹmo 2026
Davido ṣàlàyé ìdí tó fi wọ aṣọ tórúkọ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso wà lára rẹ̀ níbí ìdíje World Cup
7 Agẹmo 2026
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìjàmbá ọkọ̀ tó ṣẹlẹ̀ sí Sam Larry níbi tí ẹ̀ṣọ́ rẹ̀ Adewale ti pàdánù ẹ̀mí rẹ̀
7 Agẹmo 2026
Àdìrẹ ni ìjọ̀ba fẹ́ fi rọ́pò Kakí tó fẹ́ gbà lọ́rùn àwọn àgùnbánirọ̀ lábẹ́ àtúntò tó bá ètò ìsìnrúùlú NYSC
2 Agẹmo 2026
Àwọn ológun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gbà sẹ́nu iṣẹ́ yawọ ibùgbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní Osun, gba ọ̀pọ̀ fóònù, ohun ìní wọn - Iléeṣẹ́ ológun bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
1 Agẹmo 2026
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí jàndúkú olóṣèlú tó yìnbọn pa Ezekiel, ọmọ ọdún mẹ́rìnlá l'Osun
1 Agẹmo 2026
Wo àwọn àyípadà tí ìjọba Nàìjíríà ṣẹ̀ṣẹ̀ mú bá ìsìnrú ìlú lẹ́yìn ọdún 53 ìdásílẹ̀ rẹ̀
30 Òkùdu 2026
Wo bí ìwọ́de tako àwọn ọmọ ilẹ̀ òkèèrè ṣe gbérasọ lórílẹ̀èdè South Africa, àtàwọn agbègbè tí yóò ti wáyé
30 Òkùdu 2026
1:44
Fídíò,
Ìyà tí ọ̀rẹ́ ìyá mi tí mo gbé lọ́dọ̀ rẹ̀ lẹ́yìn ikú ìyá mi fi jẹ mí ló sọ mí di ìlúmọ̀ọ́ká alásè – Ilesanmi Mayowa, , Alásè 'Immigrant'
, Duration 1,44
30 Òkùdu 2026
Ìjọba Ondo gbẹ́sẹ̀lé èsì ìdánwò akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́tàdínlógún torí fídíò àṣemáṣe tó gba orí ayélujára
26 Òkùdu 2026
4:07
Fídíò,
Ìkà kọ́ lọmọ ejò, àwa èèyàn là ń kó tiwa bá wọn- Taiwo Okikiola-Ọmọ elejo
, Duration 4,07
26 Òkùdu 2026
Àlàyé lórí báwọn ọ̀dọ́ kan ṣe fi ipá mú abílékọ jáde ní àhámọ́ ọlọ́pàá tí wọ́n sì dáná sun ún
23 Òkùdu 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Kọmíṣọ́nà ọlọ́pàá Osun ń hùwà kò kàn mí sí rògbòdìyàn òṣèlú àti ètò ààbò tó mẹ́hẹ ní ìpínlẹ̀ náà? Ohun tí a mọ̀ rèé
16 Òkùdu 2026
3:47
Fídíò,
Ó pẹ́ tí mo ti sá kúrò nílé, mo rán ara mi ní fásitì, ọjọ́ kan làwọn òbí mi rí mi lórí Tẹlifísàn bíi gbajúmọ̀ akọrin - Shodey
, Duration 3,47
9 Òkùdu 2026
Aṣọ kan ló kù lọ́rùn àwọn òbí mi nítorí ẹ̀kọ́ mi, ètò ẹ̀yáwókàwé NELFUND ló kó mi yọ láti kẹ́kọ̀ọ́ jáde – Oladepo Gbenga akẹ́kọ̀ọ́ tó mókè jùlọ ní fásitì LAUTECH
2 Òkùdu 2026
Aṣọ oníbúrẹ́dì 500 tí mo wọ lọ síbi àmì ẹ̀yẹ AMVCA dá egbò sí mi lẹ́yìn, mú ẹ̀yìn ro mi, ó jẹ́ kí n fara ṣèṣe - Queen Mercy
29 Èbibi 2026
1:26
Fídíò,
Wo àkóbá mọ́kànlá tí ohun mímu ‘Energy Drinks’ le ṣe fún àgọ́ ara rẹ
, Duration 1,26
28 Èbibi 2026
Ìgbésẹ̀ tó dáa ni ikọ̀ Ìrù Ẹkùn ti Sunday Igboho dá sílẹ̀, àmọ́ ìbọn kò gbọdọ̀ di tọ́rọ́ fọ́n kálé láàrin ilú - Onímọ̀ ààbò
25 Èbibi 2026
Àwọn ọmọdékùnrin méjì ṣekúpa èèyàn mẹ́ta nínú mọ́ṣáláṣí, pa ara wọn lẹ́yìn rẹ̀
19 Èbibi 2026
Lẹ́yìn ò rẹyìn, Mahmoud Sadis Buba, tó mi orí ayélujára tìtì yọwọ́ nínú ètò ìdìbò 2027, ṣàlàyé ìdí abájọ
16 Èbibi 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá VCRU tuntun, ìdí fún ìdásílẹ̀ rẹ̀ àti iṣẹ́ àwọn ọlọ́pàá náà
8 Èbibi 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology