BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipinlẹ Oyo
Wo ohun tí òfin sọ nípa kí ọlọ́pàá ti ìpínlẹ̀ kan lọ gbé èèyàn nípìńlẹ̀ míràn, àti kí ẹni tí wọ́n fẹ́ mú takú
26 Ògún 2026
Àwọn ọlọ́jà ní àwọn kan ló mọ́ọ̀mọ̀ sọná sọ́jà Oranyan ní Ibadan, pè fún ìwádìí látọ̀dọ̀ ìjọ̀ba, Sarafadeen Alli ṣèlérí ìrànwọ́
25 Ògún 2026
Kí ló dé tí ìjọba àpapọ̀ yọwọ́ Makinde kúrò níbi ìfilọ́lẹ̀ òpópónà Ibadan sí Ijebu-Ode? Ohun tí a mọ̀ rèé
25 Ògún 2026
5:13
Fídíò,
Òṣìṣẹ́ báǹkì tó di ẹni tó ń ta pọ̀nmọ́ aláta lọ́jà nílùú Ibadan
, Duration 5,13
25 Ògún 2026
Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo buwọ́lu òfin gbogbo ogúnjọ́ oṣù Kẹ́jọ bíi àyájọ́ Ìṣẹ̀ṣe láì yẹ̀
20 Ògún 2026
Wo ohun mẹ́jọ pàtàkì nípa ọdún Iṣẹ̀ṣe nílẹ̀ Yorùbá tí ìjọba Oyo, Ogun àti Eko fi kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́
20 Ògún 2026
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi àyájọ́ ọdún Sango àgbáyé tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Oyo
16 Ògún 2026
0:58
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 0,58
26 Ògún 2026
Makinde lóùn ṣetán láti ṣàtúntò Nàíjíríà lọ́dún 2027
14 Ògún 2026
Má forúkọ mi ṣe ìpolongo ìbò mọ́, Makinde dá a padà fún Oriyomi
11 Ògún 2026
Obìnrin tó bá rí Olóòlù, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò gbẹ lorí ìdúró ni, èyí tó bá ya fídíò rẹ̀ bíi Wasilat láì ṣe ìràpadà, yóò kú tàbí ya wèrè láàárín ọjọ́ keje - Ìdílé Olóòlù
4 Ògún 2026
Oriyomi Hamzat kò kópa nínú ìdìbò abẹ́nú Accord, ẹ yọ ọ́ kúrò bíi olùdíje gómìnà - Busari Gudugúdù wọ́ ẹgbẹ́ òṣèlu Accord àti INEC lọ sílé-ẹjọ́
4 Ògún 2026
N kò kú o, ń kò sì ya Oloolu, àlàyé rèé lórí bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé - Wasilat
4 Ògún 2026
Ààfin Olubadan fọhùn síta lórí bí orí oyè Lekan Alabi, Abese Olubadan, ṣe sùn ìta
4 Ògún 2026
Tinubu sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ lórí ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oriire lákàtà ajínigbé, kókó ohun tó sọ rèé
31 Agẹmo 2026
DSS fi ojú afurasí márùn-ún ba ilé-ẹjọ́ lórí ìjínigbé tó wáyé l'Oyo
30 Agẹmo 2026
Bàálù tí Makinde rà kò lè nípa gidi lórí ètò ààbò l'Oyo, torí kìí ṣe irú bàálù t'awọn ẹ̀ṣọ́ elétò ààbò máa ń lò - Adeyi
30 Agẹmo 2026
Mo wà nínú ilé nígbà táwọn DSS ń yìnbọn lákọ lákọ láti pa mí, àmọ́ wọn ò rí mi - Sunday Igboho
29 Agẹmo 2026
Ìdí tí mo fi pinnu láti má báwọn jàndùkú tó jí ìyàwó mi gbé nílé ẹ̀kọ́ Esinele sọ̀rọ̀ mọ́ - Ọ̀jọ̀gbọ́n Alamu
28 Agẹmo 2026
Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù
28 Agẹmo 2026
5:16
Fídíò,
Àdó olóró àwọn ajínigbé pa Shuaibu aṣọ́gbóọba lásìkò tó ń lé àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé ní Oriire, àwọn ẹbí rẹ̀ pariwo síta
, Duration 5,16
27 Agẹmo 2026
Ẹkún sọ níbí ìsìn ìrántí fún olóògbé John Olaleye olùkọ́ Oriire táwọn jàndùkú ajínigbé ṣekúpa
26 Agẹmo 2026
APC àti Makinde ju òkò ọ̀rọ̀ lu ara wọn lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ láti dènà EFCC láti ṣe ìwádìí ìṣúná Oyo
24 Agẹmo 2026
Aláànú kan kéde láti ṣe alágbàtọ́ láéláé fún ọmọ mẹ́ta tí John Olaleye bí, olùkọ́ táwọn ajínigbé pa ní Oriire
23 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology