BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Wo àwòrán Ọmọọba Harry àti Ìyàwó rẹ̀ nígbà tí wọ́n dé sí Naijiria
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry pẹlu Iyawo rẹ lasiko ti wọn ṣe abẹwo si Naijiria
Published
11 Èbibi 2024
Àkọlé àwòrán,
Awọn eeyan n ya fọtọ pẹlu Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan, ti wọn si n ki wọn kaabọ
Àkọlé àwòrán,
Wọn fi ilẹkẹ da Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan lọla lati bu ọwọ fun wọn gẹgẹ bii eeyan nla
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Kanduna, Uba Sani ati Ọmọọba Harry nigba to ba lẹ si ipinlẹ Kaduna, ti wọn si tun fi aṣọ agbada nla da lọla.
Àkọlé àwòrán,
Awọn onijo ibilẹ fi ijo da Ọmọọba ati iyawo rẹ lara ya lasiko abẹwo.
Àkọlé àwòrán,
Gomina Uba Sani ati Ọmọọba Harry ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry ati Gomina ipinlẹ Kaduna n wo bi awọn onijo ṣe n fi ijo da wọn lara ya ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Awọn onilu ni ile ijọba
Àkọlé àwòrán,
Awọn olorin ibilẹ n fi orin da Ọmọọba lọla.
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
02:45
Fídíò,
Ìfúpá àwọn èèyàn Ayetoro l‘Ondo ń ga sí, torí bí òkun ṣe ń ya wọ ìlú, gbé iléẹ̀kọ́, ilégbèé, iléeṣẹ́, ilẹ̀ àti ibojì òkù lọ
, Duration2,45
01:26
Fídíò,
Wo àkóbá mọ́kànlá tí ohun mímu ‘Energy Drinks’ le ṣe fún àgọ́ ara rẹ
, Duration1,26
04:32
Fídíò,
Ìjì òjò líle sí òrúlé, da ògiri wó nílé ẹ̀kọ́ girama ọgbọ̀n l‘Ogbomoso, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ n kẹ́kọ̀ọ́ lábẹ́ ilé àlàpa
, Duration4,32
02:16
Fídíò,
"Ìjọba rí epo rọ̀bì ní ìlú wa àmọ́ a kò jàǹfààní kankan, kò sí omi, iná, ojú ọ̀nà, ààbò, iléẹ̀kọ́ àti ilé ìwòsàn"
, Duration2,16
03:22
Fídíò,
Àwọn ajínigbé tó kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn sí wa nígbà tí a ń lé wọn wọgbó ìbọn wà kò ràn wọ́n ni – Àwọn ọlọ́dẹ ìlú Esinele
, Duration3,22
02:31
Fídíò,
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Ebola tuntun
, Duration2,31
02:34
Fídíò,
Oronna, jagunjagun tó gbéra láti Oyo lọ tẹ ìlú Ilaro dó
, Duration2,34
02:21
Fídíò,
Olaniyan 'Idamu Industry' Oluwatosin jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí ètò 'Ṣé o láyà?'
, Duration2,21
05:24
Fídíò,
Agbolé Akọni: Mọ̀ nípa Ogboriefon, akọni tí wọ́n rí he lórí àkìtàn tó di jagunjagun ńlá
, Duration5,24
01:40
Fídíò,
Wo bí hòmóònù ṣe ń mú àyípadà bá ìhùwàsí àwọn obìnrin ní ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀
, Duration1,40
04:05
Fídíò,
Mo ti fẹ́ obìnrin rí lágbo tíátà àmọ́ kò ní àṣeyọrí, owó, obìnrin àti agbára ló ń fa gbajúmọ̀ ọkùnrin ṣubú - Abayomi Alvin
, Duration4,05
01:02
Fídíò,
Sola Sobowale àti Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí àmì ẹ̀yẹ AMVCA tí wọn gbà
, Duration1,02
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìfẹ̀hónúhàn bẹ́ sílẹ̀ ní France lẹ́yìn tí PSG gba ife ẹ̀yẹ Champions League, èèyàn 219 farapa
31 Èbibi 2026
Makinde ṣàbẹ̀wò sẹ́bí àwọn èèyàn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, ọkọ Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n gbé bú sẹ́kún
31 Èbibi 2026
Agbébọn jí ajagunfẹ̀yìntì àti ìyàwọ rẹ̀ gbé ní Katsina
31 Èbibi 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Télọ̀ kan ju èké fídíò nípa ìkọlù agbébọn l‘Ogun sórí ayélujára láti pawó, ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ fún-un
26 Èbibi 2026
Ìgbésẹ̀ tó dáa ni ikọ̀ Ìrù Ẹkùn ti Sunday Igboho dá sílẹ̀, àmọ́ ìbọn kò gbọdọ̀ di tọ́rọ́ fọ́n kálé láàrin ilú - Onímọ̀ ààbò
25 Èbibi 2026
"Ìṣọ́ òru ní ṣọ́ọ́sì àti mọ́ṣáláṣí dópin, ìsìn kò gbọdọ̀ ju wákàtí méjì lọ, káwọn ṣọ́ọ̀ṣì tó wà ní ìgbéríkò sì kó wá sáàrin ìlú torí ìkọlù agbébọn"
25 Èbibi 2026
Saudi yóò ṣe ògbufọ̀ wáàsí ọjọ́ Arafa Hajj ọdún yìí sí Yorùbá, Hausa àti èdè mẹ́tàlélọ́gbọ̀n míì
22 Èbibi 2026
Afeez Owo ṣàlàyé ohun tó fa ìyapa láàrin òun àti Mide lásìkò kan nínú ìgbéyàwó wọn
21 Èbibi 2026
Ohun tó ṣẹlẹ̀ rèé níbi ìdìbò abẹ́nú APC sípò Gómìnà l'Oyo
21 Èbibi 2026
"Òfin tó mú Eleha ló mú eléégún, ẹ fààyè gbàwọn ẹlẹ́sìn àbáláyé náà láti máa wọ aṣọ ìbílẹ̀ lọ ilé ẹ̀kọ́ ISI n'Ibadan"
21 Èbibi 2026
Sunday Igboho ṣe àfihàn ẹ̀ṣọ́ ààbò "Ija Ekun" tó fẹ́ fi kojú àwọn agbébọn nílẹ̀ Yorùbá bí ìjọba bá fún-un láṣẹ
21 Èbibi 2026
Makinde ṣàgbédìde òfin tó de àwọn fijilanté àtàwọn ẹ̀ṣọ́ ààbò abẹ́nú míì
21 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Makinde ṣàbẹ̀wò sẹ́bí àwọn èèyàn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, ọkọ Ọ̀gá ilé ẹ̀kọ́ tí wọ́n gbé bú sẹ́kún
2
''Tí ìjọba bá lè gba ọmọ Yoruba láyè láti lo ìlànà ti ìbílẹ̀, ilẹ̀ wa yóò bọ́ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀mí''
3
Ẹgbẹ́ àwọn gómìnà bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti máa san ₦100,000 gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ
4
Ìfẹ̀hónúhàn bẹ́ sílẹ̀ ní France lẹ́yìn tí PSG gba ife ẹ̀yẹ Champions League, èèyàn 219 farapa
5
Ọlọ́pàá méjì kú ní ìpínlẹ̀ Osun lẹ́yìn tí ọkọ̀ gbá wọn lójú pópó
6
Agbébọn jí ajagunfẹ̀yìntì àti ìyàwọ rẹ̀ gbé ní Katsina
7
Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé
8
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́jọ lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dáná sun ilé ẹkọ̀ tí akẹgbẹ́ wọn 16 ti kú
9
Seyi Makinde ni yóò ṣojú wa nínú ètò ìdìbò Ààrẹ ọdún 2027 – Ẹgbẹ́ òṣèlú APM
10
Ta ni Joel Adesiyan, olùkọ́ táwọn agbébọn pa l'Ogbomoso, àti pé, ṣé òun ni wọ́n pa ní àhámọ́ àwọn ajínigbé?
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology