BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Wo àwòrán Ọmọọba Harry àti Ìyàwó rẹ̀ nígbà tí wọ́n dé sí Naijiria
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry pẹlu Iyawo rẹ lasiko ti wọn ṣe abẹwo si Naijiria
Published
11 Èbibi 2024
Àkọlé àwòrán,
Awọn eeyan n ya fọtọ pẹlu Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan, ti wọn si n ki wọn kaabọ
Àkọlé àwòrán,
Wọn fi ilẹkẹ da Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan lọla lati bu ọwọ fun wọn gẹgẹ bii eeyan nla
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Kanduna, Uba Sani ati Ọmọọba Harry nigba to ba lẹ si ipinlẹ Kaduna, ti wọn si tun fi aṣọ agbada nla da lọla.
Àkọlé àwòrán,
Awọn onijo ibilẹ fi ijo da Ọmọọba ati iyawo rẹ lara ya lasiko abẹwo.
Àkọlé àwòrán,
Gomina Uba Sani ati Ọmọọba Harry ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry ati Gomina ipinlẹ Kaduna n wo bi awọn onijo ṣe n fi ijo da wọn lara ya ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Awọn onilu ni ile ijọba
Àkọlé àwòrán,
Awọn olorin ibilẹ n fi orin da Ọmọọba lọla.
Ṣawari síi
Orilẹede Naijiria
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
05:13
Fídíò,
Òṣìṣẹ́ báǹkì tó di ẹni tó ń ta pọ̀nmọ́ aláta lọ́jà nílùú Ibadan
, Duration5,13
03:37
Fídíò,
Ǹjẹ́ ó tọ́ kí òbí máa kàn án ní dandan f'áwọn ọmọ láti tọ́jú wọn lọ́jọ́ ogbó?
, Duration3,37
05:53
Fídíò,
Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan
, Duration5,53
02:30
Fídíò,
Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa
, Duration2,30
02:54
Fídíò,
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n Ademola Adeleke ti já àkóso ìjọba Osun gbà mọ́ ọ lọ́wọ́? Àlàyé rèé
, Duration2,54
05:26
Fídíò,
Àwọn dókítà ti sọ fún mi pé kí n dẹ́kun sígà fífà àti ọtí mímu-Tope Osoba. Nibo Laye Koju Si?
, Duration5,26
02:30
Fídíò,
Nǹkan kan tí mo mọ̀ ni pé bí orin tí mo bá kọ bá bùkún fún mi, yóò bùkún fún gbogbo èèyàn tó bá gbọ́ ọ - Bisi Manuel
, Duration2,30
03:24
Fídíò,
Àwọn olólùfẹ́ Kola Oyewo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lẹ́yìn ìsìnkú rẹ̀
, Duration3,24
04:02
Fídíò,
Àwọn sinimá kan wà tí mo ṣe tí àwọn òbí mi kò lè wò nítorí… - Bolaji Ogunmola, òṣèré tíátà
, Duration4,02
02:58
Fídíò,
Ghana must go: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa báàgì yìí àti bó ṣe gbajúmọ̀ ní Naijiria
, Duration2,58
04:47
Fídíò,
"Àgọ́ NYSC ni mo ti ń bọ̀, tí mo fi kò ìjàmbá, n kò le dá jókòó, rìn, sùn, yàgbẹ́ tàbí tọ̀, tí mo bá tún ayé wa, n kò ní sìnrú ìlú mọ́"
, Duration4,47
03:38
Fídíò,
À ti tún àwọn ẹ̀rọ̀ BVAS wa ṣe láti dènà kí èèyàn kan lo káàdì ìdìbò ẹlòmíràn nínú ìdìbò gómìna l‘Osun - Alága INEC
, Duration3,38
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
A ti ṣetán láti ṣàtìlẹ́yìn fún ìjọba lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ – OPC
30 Ògún 2026
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti ṣọ́ owó ná lórí oúnjẹ lásìkò ọ̀wọ́ngógó yìí
30 Ògún 2026
Kí ló mú kí ọkùnrin kan fi ọ̀bẹ pa èèyàn kan nílé sinimá l'Eko, tí ẹ̀mí òun náà fi bọ́? Àlàyé rèé
30 Ògún 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Bí o ṣe lè di olówó gọbọi nípa títú àṣírí àwọn tó ń jí owó ìlú kó lọ sókè òkun
27 Ògún 2026
Tani Olohun ṣàlàyé ohun tó mú Sunday Igboho wá sílé rẹ̀, àti ọ̀rọ̀ tó bá ọ̀gá ọlọ́pàá Kwara sọ káwọn ọlọ́pàá tó wá fipá gbé e nílé tó lè kúrò lágbègbè rẹ̀
27 Ògún 2026
Bílíọ̀nù mẹ́jọ Naira làwọn ajínigbé ti gbà lọ́wọ́ aráàlú láàrín ọdún 2025 sí 2026 - Ìwádìí
27 Ògún 2026
Àwọn wo ni ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Black Axe' tí ọlọ́pàá àgbáyé mú fún jìbìtì orí ayélujéra káàkiri àgbáyé àti ní ìwọ̀ oòrùn Africa? Àlàyé rèé
27 Ògún 2026
Ètò ìsìnkú ti bẹ̀rẹ̀ fún Taiwo Hassan 'Ogogo'
26 Ògún 2026
Àwọn ọmọ Africa wà nínú àwọn tí wọ́n ń wá níbi àjálù ilẹ̀ rírì tó ti gbẹ̀mí èèyàn tó lé ní 160 ní Nepal, èèyàn 800 míràn di àwátì
27 Ògún 2026
Iná sọ níléèwòsàn, ọmọ ìkókó mẹ́rìnlá jóná mọ́lé
26 Ògún 2026
Ọlọ́pàá ṣàwárí ilé tí wọ́n ti ń ta ọmọ ní Mowe, tú àwọn olóyún àti ọmọdé sílẹ̀
26 Ògún 2026
Olubadan sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC
25 Ògún 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Wo ìdí pàtàkí mẹ́rin tí Ààrẹ Tinubu kò ṣe fẹ́ kí ilẹ̀ Amẹ́ríkà fí àkọsílẹ̀ rẹ̀ nípà egbòogi olóró síta
2
Gómìnà Adeleke, mo kí ẹ kú oríire pé o wọlé fún sáà kejì àmọ́ ọ̀rọ̀ sì kù lẹ́yìn rẹ̀ - Oyebamiji, olùdíje gómìnà APC l'Osun
3
Àlàyé ohun tó fa ilẹ̀ rírì Nepal tó mú ẹ̀mí èèyàn 700 lọ
4
Ọbalayé tó kéré jùlọ lágbáyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 34
5
Kí ló mú kí ọkùnrin kan fi ọ̀bẹ pa èèyàn kan nílé sinimá l'Eko, tí ẹ̀mí òun náà fi bọ́? Àlàyé rèé
6
Oṣù mẹ́fà nínú ọdún ni mo fi ń ṣiṣẹ́ l’Amẹrika, owó rẹ̀ ni mo fi ń tún ìlú ṣe - Onidera
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 18 Ẹrẹ̀nà 2024
7
Ariwo sọ pé Aunty Ramota ṣe iṣẹ abẹ láti fọn idi, ó ti dákú láì jẹ́ aráayé tàbí èrò ọ̀run, Ijoba Lande ṣàlàyé bí ọ̀rọ̀ ṣe jẹ́
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 10 Òkùdu 2024
8
Wo ọ̀nà àrékérekè tuntun táwọn agbésùnmọ̀mí ń gbà r'owó ní Naijiria bàyìí yàtọ̀ sí gbígba owó ìtúsílẹ̀
9
A ti ṣetán láti ṣàtìlẹ́yìn fún ìjọba lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ – OPC
10
Àìsàn jẹjẹrẹ kọlu àgbà òṣèrè mííràn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology