BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Coronavirus: Báyìí ni nkan ṣe n lọ ní pápákọ̀ ọkọ̀ òfurufú l'Eko lẹ́yìn tí Coronavirus wọ́lé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo awọn to n wọle, tabi jade kuro ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed lo n gba abẹ ayẹwo kọja
29 Èrèlè 2020
Àkọlé àwòrán,
Yatọ si irinṣẹ ti wọn n mu dani, ẹrọ kan tun wa bi kamẹra to n ṣe ayẹwo awọn eero baalu fun apẹẹrẹ aarun Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Oriṣiriṣi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo wa ni ikalẹ ni papakọ ofurufu ilu Eko fun ayẹwo awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Koda, wọn gbe omi aporo kokoro aifojuri 'sanitizer' silẹ fun awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Ati oṣiṣẹ ati eero baalu lo n lo iboju lati ba ara wọn sọrọ nitori Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Kii ṣe ita papakọ ofurufu nikan ni ikiyesara ti n waye, gbagbaagba ni kaluku n boju-bomu ninu ọfiisi.
Àkọlé àwòrán,
Ẹrọ ayaworan wa tun gbe oṣiṣẹ eto ilera kan to wa lẹnu iṣẹ t'oun ti iboju ati ìbọ̀wọ́
Àkọlé àwòrán,
Ṣugbọn o, Coronavirus ko da wiwọle ati jijade ni Naijiria duro ni papakọ ofurufu naa. Kẹti-kẹti ni eero n ya lati wọ baalu.
Àkọlé àwòrán,
Igbesẹ oju lalakan fi n sọri ọhun ko yọ awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde (Immigration) silẹ. Iboju lawọn naa fi ṣe koju o ma ri ibi.
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
02:33
Fídíò,
Ẹni tó bá ní kò sí ayé, ayé wà o, ohun tó jẹ mọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀mí wà nínú iṣẹ́ tíátà - Tosin Olaniyan
, Duration2,33
01:25
Fídíò,
Kí ló sọ àwọn ológbò di gbajúmọ̀ orí ayélujára ní Instabul?
, Duration1,25
03:16
Fídíò,
Kí ni ẹ̀ṣẹ̀ wa ní Ido-Ani, tí ìjọba Ondo fi pa wá tì láìsí ilé ìwòsàn àti ojú ọ̀nà tó dára? – Aráàlú fárígá
, Duration3,16
04:12
Fídíò,
Àwọn òṣèré òde òní nílò láti máa ṣàgbéyẹ̀wò ìtàn tí wọ́n ń kọ, a kìí ṣe eégún oníhòhò - Lere Paimo
, Duration4,12
06:34
Fídíò,
Ọba Ido-Osun pàṣe kí wọ́n ti ilé ìjọsìn tí pásítọ̀ rẹ̀ lọ gbàdúrà lójúbọ Osun Osogbo pa
, Duration6,34
05:05
Fídíò,
Kí ni ohun abàmì tó wà nínú Omi Oko ní Ilesa, tí wọn ṣe kọ́lé fún-un, yọ fèrèsé àti ìlẹ̀kùn sí?
, Duration5,05
04:00
Fídíò,
Ìwé mẹ́fà ni mo kà, kí ń tó kọ́ iṣẹ́ Rédíóníìkì, ipasẹ̀ ẹgbọ́n mi kan níbẹ̀ ni mo gbà dé ìdí iṣẹ́ tíátà - Okele
, Duration4,00
04:32
Fídíò,
"Mo ra ‘Sim Card’ táwọn ajínigbé ti fi gbá owó ìtúsílẹ̀ N50m, pa ẹni tí wọn jí gbé, mo bá dèrò àtìmọ́lé"
, Duration4,32
01:13
Fídíò,
Mọ̀ nípa àwọn ewu méje tó rọ̀ mọ́ ṣíṣe ìdí ńlá, BBL, àti ìlànà tí wọ́n ń gbà ṣe é
, Duration1,13
01:03
Fídíò,
Àwọn ọ̀dọ̀ ilẹ̀ Africa ni ìlera ọpọlọ wọn pé jù lọ láàgbáyé-Ìwádìí
, Duration1,03
01:57
Fídíò,
DJ Cuppy ṣàlàyé ìdí tí inú rẹ̀ fi dùn pé Ààrẹ Tinubu ṣàbẹ̀wò sí ilẹ̀ UK
, Duration1,57
Ìròyìn tó ṣe kókó
Bí àjọ INEC kò ṣe yọjú síbi ìpàdé àpapọ̀ ADC, àwọn àṣaájú ẹgbẹ́ sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Tinubu, lé adarí igun alátakò méjì
ìṣẹ́jú 3 sẹ́yìn
Àbọ̀ ìwádìí BBC lórí ikú ìyàwó Wòlíì olùdásílẹ̀ ìjọ tó ń ṣe ọ̀pọ̀ èèyàn ní kàyééfì
wákàtí 2 sẹ́yìn
"Bí Ishmail tí iná gbé ní Ilorin ṣe ń kàwé, ló ń ṣiṣẹ́ láti jẹ́ èèyàn láyé, owó díẹ̀ tó rí ló fi ra Kọ̀ǹpútà tó gbiná"
ìṣẹ́jú 34 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Wo bí o ṣe lè wo, tàbí ṣe àtẹ̀jáde ìwé atọ́nà pélébé fún ìdánwò Jamb UTME
10 Ìgbé 2026
Ta ni ọ̀gágun Braimah táwọn agbésùnmọ̀mí ṣekúpa pẹ̀láwọn ọmọogun míràn ní Borno, Tinubu kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn tó ṣubú lójú ìjà?
10 Ìgbé 2026
Soun Ogbomoso ti pín ìlú yẹ́lẹyẹ̀lẹ pẹ̀lú ìwà kíìgbọ́-kìígbà rẹ̀, èmi ò sì lè báa ṣiṣẹ́ mọ́ ni mo ṣe kọ̀wé fipò Máyégún sílẹ̀ -Sẹ́nétọ̀ Adeseun
10 Ìgbé 2026
Ìjọba àpapọ̀ ké gbàjarè lẹ́yìn tí àrùn tó ń gbẹ̀mí màlúù kọlu ìpínlẹ̀ 17
10 Ìgbé 2026
Àlàyé lórí ohun tó fa rògbòdìyàn inú ẹgbẹ́ ADC, èyí tó jẹ́ kí INEC yẹ àga máwọn adarí ẹgbẹ́ náà nídìí
9 Ìgbé 2026
Ẹ múra o! Òjò ńlá tó le fa àgbárá òjò ń bọ̀ ní ìpínlẹ̀ mẹ́wàá - NiMet
9 Ìgbé 2026
Amẹ́ríkà gbé ìkìlọ̀ tuntun jáde lórí ọ̀rọ̀ àbò ní Nàìjíríà, Ó ní ìlú Abuja àtàwọn ìpínlẹ̀ 23 kan ti di ibi àìgbọdọ̀ wọ̀ fáwọn èèyàn rẹ̀, ìdí rèé
9 Ìgbé 2026
Akẹ́kọ̀ọ́ Covenant University jáde láyé níbi tó ti ń gbá bọ́ọ̀lù, Ilé ẹ̀kọ́ ṣàlàyé ohun tó fa ikú rẹ̀
9 Ìgbé 2026
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ aláàbò ilẹ̀ Ibadan tuntun, Ibadan Community Guard
9 Ìgbé 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Dárúkọ pẹ̀lú ẹ̀rí tó dájú àwọn tó fi rìbá lọ̀ ọ́ láti gbé ìgbésẹ̀ ìyọnípọ̀ Makinde bíbẹ́ẹ̀kọ́... - Olórí ilé aṣòfin àná
2
Àbọ̀ ìwádìí BBC lórí ikú ìyàwó Wòlíì olùdásílẹ̀ ìjọ tó ń ṣe ọ̀pọ̀ èèyàn ní kàyééfì
3
Àwọn ìdí rèé tí gómìnà kan fi le yọ ọba nípò lábẹ́ òfin
4
Bí àjọ INEC kò ṣe yọjú síbi ìpàdé àpapọ̀ ADC, àwọn àṣaájú ẹgbẹ́ sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Tinubu, lé adarí igun alátakò méjì
5
Lẹ́yìn ìwọ́de tako ìjínigbé, Aiyedatiwa ṣàbẹ̀wò sáwọn agbègbè tí ààbò ti mẹ́hẹ, ó ní ajínigbé 100 tó ń ṣọṣẹ́ l‘Ondo ní ọwọ́ ti bà
6
Ìdí rèé tí Iyabo Obasanjo ṣe gba kámú bí gbogbo ẹgbẹ́ APC l‘Ogun ṣe fa Yayi kalẹ̀ bíi olùdíje gómìnà
7
Ìjọba gbẹ́sẹ̀ lé dúkìá afurasí mẹ́tàlá tó ń ṣagbátẹrù ìgbésùnmọ̀mí
8
Wo ìpínlẹ̀ méje tí yóò wà nínú òkùnkùn birimù fún ọ̀sẹ̀ mẹ́fà
9
Àwọn ọmọ Iran kọminú lórí bóyá ogun Amẹ́ríkà lè tẹ̀síwájú tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́ lẹ́yìn tí ìpàdé àláfíà forí ṣánpọ́n
10
Ọkọ̀ tó kó àwọn agbábọ́ọ̀lù pàdé àwọn adigunjalè lọ́nà, wọ́n yìnbọn pa agbábọ́ọ̀lù kan
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology