BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Coronavirus: Báyìí ni nkan ṣe n lọ ní pápákọ̀ ọkọ̀ òfurufú l'Eko lẹ́yìn tí Coronavirus wọ́lé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo awọn to n wọle, tabi jade kuro ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed lo n gba abẹ ayẹwo kọja
Published
29 Èrèlè 2020
Àkọlé àwòrán,
Yatọ si irinṣẹ ti wọn n mu dani, ẹrọ kan tun wa bi kamẹra to n ṣe ayẹwo awọn eero baalu fun apẹẹrẹ aarun Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Oriṣiriṣi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo wa ni ikalẹ ni papakọ ofurufu ilu Eko fun ayẹwo awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Koda, wọn gbe omi aporo kokoro aifojuri 'sanitizer' silẹ fun awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Ati oṣiṣẹ ati eero baalu lo n lo iboju lati ba ara wọn sọrọ nitori Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Kii ṣe ita papakọ ofurufu nikan ni ikiyesara ti n waye, gbagbaagba ni kaluku n boju-bomu ninu ọfiisi.
Àkọlé àwòrán,
Ẹrọ ayaworan wa tun gbe oṣiṣẹ eto ilera kan to wa lẹnu iṣẹ t'oun ti iboju ati ìbọ̀wọ́
Àkọlé àwòrán,
Ṣugbọn o, Coronavirus ko da wiwọle ati jijade ni Naijiria duro ni papakọ ofurufu naa. Kẹti-kẹti ni eero n ya lati wọ baalu.
Àkọlé àwòrán,
Igbesẹ oju lalakan fi n sọri ọhun ko yọ awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde (Immigration) silẹ. Iboju lawọn naa fi ṣe koju o ma ri ibi.
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
05:13
Fídíò,
Òṣìṣẹ́ báǹkì tó di ẹni tó ń ta pọ̀nmọ́ aláta lọ́jà nílùú Ibadan
, Duration5,13
03:37
Fídíò,
Ǹjẹ́ ó tọ́ kí òbí máa kàn án ní dandan f'áwọn ọmọ láti tọ́jú wọn lọ́jọ́ ogbó?
, Duration3,37
05:53
Fídíò,
Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan
, Duration5,53
02:30
Fídíò,
Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa
, Duration2,30
02:54
Fídíò,
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n Ademola Adeleke ti já àkóso ìjọba Osun gbà mọ́ ọ lọ́wọ́? Àlàyé rèé
, Duration2,54
05:26
Fídíò,
Àwọn dókítà ti sọ fún mi pé kí n dẹ́kun sígà fífà àti ọtí mímu-Tope Osoba. Nibo Laye Koju Si?
, Duration5,26
02:30
Fídíò,
Nǹkan kan tí mo mọ̀ ni pé bí orin tí mo bá kọ bá bùkún fún mi, yóò bùkún fún gbogbo èèyàn tó bá gbọ́ ọ - Bisi Manuel
, Duration2,30
03:24
Fídíò,
Àwọn olólùfẹ́ Kola Oyewo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lẹ́yìn ìsìnkú rẹ̀
, Duration3,24
04:02
Fídíò,
Àwọn sinimá kan wà tí mo ṣe tí àwọn òbí mi kò lè wò nítorí… - Bolaji Ogunmola, òṣèré tíátà
, Duration4,02
02:58
Fídíò,
Ghana must go: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa báàgì yìí àti bó ṣe gbajúmọ̀ ní Naijiria
, Duration2,58
04:47
Fídíò,
"Àgọ́ NYSC ni mo ti ń bọ̀, tí mo fi kò ìjàmbá, n kò le dá jókòó, rìn, sùn, yàgbẹ́ tàbí tọ̀, tí mo bá tún ayé wa, n kò ní sìnrú ìlú mọ́"
, Duration4,47
03:38
Fídíò,
À ti tún àwọn ẹ̀rọ̀ BVAS wa ṣe láti dènà kí èèyàn kan lo káàdì ìdìbò ẹlòmíràn nínú ìdìbò gómìna l‘Osun - Alága INEC
, Duration3,38
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìdí rèé tí Dangote fi ṣe àfikún owó epo bẹntiróòlù fún ìgbà mẹ́ta láàrin ọ̀sẹ̀ kan àti ipa rẹ̀ lórí aráàlú
wákàtí 8 sẹ́yìn
Àwọn ọmọ ogun wa nílẹ̀ Áfríkà ló dìde ìrànlọ́wọ́ láti kojú ìdìtẹ̀gbàjọba tó fẹ́ẹ́ wáyé ní Niger - Russia ṣàlàyé
wákàtí 8 sẹ́yìn
Lóòtọ́ọ́ ni Ogogo gbé ₦25m fún mi, àmọ́ kò wà fún kíkọ́ mọ́ṣáláṣí, ohun tó ní kí ń fi owó náà ṣe rèé - Ìmáàmù àgbà Ilaro
wákàtí 9 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Bí o ṣe lè di olówó gọbọi nípa títú àṣírí àwọn tó ń jí owó ìlú kó lọ sókè òkun
27 Ògún 2026
Tani Olohun ṣàlàyé ohun tó mú Sunday Igboho wá sílé rẹ̀, àti ọ̀rọ̀ tó bá ọ̀gá ọlọ́pàá Kwara sọ káwọn ọlọ́pàá tó wá fipá gbé e nílé tó lè kúrò lágbègbè rẹ̀
27 Ògún 2026
Bílíọ̀nù mẹ́jọ Naira làwọn ajínigbé ti gbà lọ́wọ́ aráàlú láàrín ọdún 2025 sí 2026 - Ìwádìí
27 Ògún 2026
Àwọn wo ni ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Black Axe' tí ọlọ́pàá àgbáyé mú fún jìbìtì orí ayélujéra káàkiri àgbáyé àti ní ìwọ̀ oòrùn Africa? Àlàyé rèé
27 Ògún 2026
Ètò ìsìnkú ti bẹ̀rẹ̀ fún Taiwo Hassan 'Ogogo'
26 Ògún 2026
Àwọn ọmọ Africa wà nínú àwọn tí wọ́n ń wá níbi àjálù ilẹ̀ rírì tó ti gbẹ̀mí èèyàn tó lé ní 160 ní Nepal, èèyàn 800 míràn di àwátì
27 Ògún 2026
Iná sọ níléèwòsàn, ọmọ ìkókó mẹ́rìnlá jóná mọ́lé
26 Ògún 2026
Ọlọ́pàá ṣàwárí ilé tí wọ́n ti ń ta ọmọ ní Mowe, tú àwọn olóyún àti ọmọdé sílẹ̀
26 Ògún 2026
Olubadan sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC
25 Ògún 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Lóòtọ́ọ́ ni Ogogo gbé ₦25m fún mi, àmọ́ kò wà fún kíkọ́ mọ́ṣáláṣí, ohun tó ní kí ń fi owó náà ṣe rèé - Ìmáàmù àgbà Ilaro
2
Kí ló ṣe Adewale Eleso, gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó fi ṣiṣẹ́ abẹ, ipò wo sì ni ìlera rẹ̀ wà?
3
Àìsàn jẹjẹrẹ kọlu àgbà òṣèrè mííràn
4
Ṣé lóòótọ́ ni Kira, ọmọ Ogogo bímọ tuntun? Mọ̀lẹ́bí Ogogo sọ̀rọ̀ síta
5
Ìdí rèé tí Dangote fi ṣe àfikún owó epo bẹntiróòlù fún ìgbà mẹ́ta láàrin ọ̀sẹ̀ kan àti ipa rẹ̀ lórí aráàlú
6
A sa gbogbo ipá wa láti gba ẹ̀mí Ogogo là – Yayi
7
Ètò ìsìnkú ti bẹ̀rẹ̀ fún Taiwo Hassan 'Ogogo'
8
Tani Olohun ṣàlàyé ohun tó mú Sunday Igboho wá sílé rẹ̀, àti ọ̀rọ̀ tó bá ọ̀gá ọlọ́pàá Kwara sọ káwọn ọlọ́pàá tó wá fipá gbé e nílé tó lè kúrò lágbègbè rẹ̀
9
Àwọn ọmọ ogun wa nílẹ̀ Áfríkà ló dìde ìrànlọ́wọ́ láti kojú ìdìtẹ̀gbàjọba tó fẹ́ẹ́ wáyé ní Niger - Russia ṣàlàyé
10
Wo àwọn òṣèré tíátà Yoruba méje tó jáde láyé lọ́dún 2026
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology